Àwọn Adájọ́ 18:29 BM

29 Wọ́n yí orúkọ ìlú náà pada kúrò ní Laiṣi tí ó ń jẹ́ tẹ́lẹ̀, wọ́n sọ ọ́ ní Dani gẹ́gẹ́ bí orúkọ baba ńlá wọn tí ó jẹ́ ọmọ bíbí Israẹli.

Ka pipe ipin Àwọn Adájọ́ 18

Wo Àwọn Adájọ́ 18:29 ni o tọ