Àwọn Adájọ́ 2:4 BM

4 Nígbà tí Angẹli OLUWA sọ ọ̀rọ̀ yìí fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn.

Ka pipe ipin Àwọn Adájọ́ 2

Wo Àwọn Adájọ́ 2:4 ni o tọ