Àwọn Adájọ́ 9:19 BM

19 Nítorí náà, bí ó bá jẹ́ pé pẹlu òtítọ́ inú, ati ọ̀nà ẹ̀tọ́ ni ẹ fi ṣe ohun tí ẹ ṣe sí Gideoni ati ìdílé rẹ̀ lónìí, ẹ máa yọ̀ lórí Abimeleki kí òun náà sì máa yọ̀ lórí yín.

Ka pipe ipin Àwọn Adájọ́ 9

Wo Àwọn Adájọ́ 9:19 ni o tọ