Àwọn Adájọ́ 9:31 BM

31 Ó ranṣẹ sí Abimeleki ní Aruma, ó ní, “Gaali, ọmọ Ebedi, ati àwọn arakunrin rẹ̀ ti dé sí Ṣekemu, wọn kò sì ní gbà fún ọ kí o wọ ibí mọ́.

Ka pipe ipin Àwọn Adájọ́ 9

Wo Àwọn Adájọ́ 9:31 ni o tọ