Àwọn Adájọ́ 13:20 BM

20 Nígbà tí ọwọ́ iná ẹbọ náà bẹ̀rẹ̀ sí yọ sókè láti orí pẹpẹ, angẹli OLUWA náà bẹ̀rẹ̀ sí gòkè lọ ninu ọwọ́ iná orí pẹpẹ náà, bí Manoa ati iyawo rẹ̀ ti ń wò ó. Wọ́n bá dojú wọn bolẹ̀.

Ka pipe ipin Àwọn Adájọ́ 13

Wo Àwọn Adájọ́ 13:20 ni o tọ