Àwọn Adájọ́ 13:24 BM

24 Nígbà tí ó yá, obinrin náà bí ọmọkunrin kan, ó sì sọ ọ́ ní Samsoni. Ọmọ náà bẹ̀rẹ̀ sí dàgbà, OLUWA sì bukun un.

Ka pipe ipin Àwọn Adájọ́ 13

Wo Àwọn Adájọ́ 13:24 ni o tọ