Àwọn Adájọ́ 15:14 BM

14 Nígbà tí ó dé Lehi, àwọn Filistia wá hó pàdé rẹ̀. Ẹ̀mí OLUWA bà lé Samsoni tagbára tagbára, okùn tí wọ́n fi dè é sì já bí ìgbà tí iná ràn mọ́ fọ́nrán òwú. Gbogbo ìdè tí wọ́n fi dè é já kúrò ní ọwọ́ rẹ̀.

Ka pipe ipin Àwọn Adájọ́ 15

Wo Àwọn Adájọ́ 15:14 ni o tọ