Àwọn Adájọ́ 9:36 BM

36 Nígbà tí Gaali rí wọn, ó sọ fún Sebulu pé, “Wò ó, àwọn eniyan kan ń sọ̀kalẹ̀ bọ̀ láti orí òkè.”Sebulu dá a lóhùn pé, “Òjìji òkè ni ò ń wò tí o ṣebí eniyan ni.”

Ka pipe ipin Àwọn Adájọ́ 9

Wo Àwọn Adájọ́ 9:36 ni o tọ