Rutu 4:17 BM

17 Àwọn obinrin àdúgbò bá sọ ọmọ náà ní Obedi, wọ́n ń sọ káàkiri pé, “A bí ọmọkunrin kan fún Naomi.” Obedi yìí ni baba Jese tíí ṣe baba Dafidi.

Ka pipe ipin Rutu 4

Wo Rutu 4:17 ni o tọ