21 Ọwọ́ ara mi ni èmi Paulu fi kọ gbolohun ìkíni yìí.
22 Bí ẹnikẹ́ni kò bá fẹ́ràn Oluwa wa, ẹni ègún ni! Marana ta–Oluwa wa, máa bọ̀!
23 Kí oore-ọ̀fẹ́ Oluwa wa Jesu kí ó wà pẹlu yín.
24 Mo fi ìfẹ́ kí gbogbo yín ninu Kristi Jesu.