Jóṣúà 6:2 BMY

2 Nígbà náà ni Olúwa wí fún Jóṣúà pé, “Wò ó, mo ti fi Jẹ́ríkò lé ọ lọ́wọ́ pẹ̀lú ọba rẹ̀ àti àwọn jagunjagun rẹ̀.

Ka pipe ipin Jóṣúà 6

Wo Jóṣúà 6:2 ni o tọ