Àwọn Hébérù 4:1 BMY

1 Nítorí náà, gẹ́gẹ́ bí Ọlọ́run ti ṣe ìlérí àti wọ inú ìsinmi rẹ̀ fún wa, ẹ jẹ́ kí á bẹ̀rù, kí ẹnikẹ́ni nínú yín má baà dà bí ẹni pé ó tí kùnà rẹ̀.

Ka pipe ipin Àwọn Hébérù 4

Wo Àwọn Hébérù 4:1 ni o tọ