21 Ṣùgbọ́n Ábíṣáì ọmọ Serúíà dáhùn ó sì wí pé, “Kò há tọ́ kí a pa Síméì nítorí èyí? Nítorí pé òun ti bú ẹni àmì òróró Olúwa.”
Ka pipe ipin 2 Sámúẹ́lì 19
Wo 2 Sámúẹ́lì 19:21 ni o tọ