1 Nígbà tí ọmọ Ṣọ́ọ̀lù sì gbọ́ pé, Ábínérì kú ní Hébírónì, ọwọ́ rẹ̀ sì rọ, gbogbo Ísírẹ́lì sì rẹ̀wẹ̀sì.
Ka pipe ipin 2 Sámúẹ́lì 4
Wo 2 Sámúẹ́lì 4:1 ni o tọ