10 Jéúṣì Ṣákíà àti Mírímà. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin Rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
11 Nípaṣẹ̀ Húṣímù ó ní Ábítúbù àti Élípálì.
12 Àwọn ọmọ Élípálì:Ébérì, Míṣámì, Ṣémédù (ẹni tí ó kọ́ Ónò àti Lódì pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká Rẹ̀.)
13 Pẹ̀lú Béríà àti Ṣémà, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Áíjálónì àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gátì kúrò.
14 Áhíò, Ṣásákì Jérémílò,
15 Ṣébádíà, Árádì, Édérì
16 Míkáélì Íṣífà àti Jóhà jẹ́ àwọn ọmọ Béríà.