10 Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé:“Kò sí ẹni tí í ṣe olódodo, kò sí ẹnìkan
11 Kò sí ẹni tí òye yé,kò sí ẹni tí ó ń wá Ọlọ́run.
12 Gbogbo wọn ni ó ti yapa,wọ́n jùmọ̀ di aláìlérè;kò sí ẹni tí ń ṣe rere,kò tilẹ̀ sí ẹnìkan.”
13 “Ibojì tí ó ṣí sílẹ̀ ní Ọ̀fun wọn:ahọ́n wọn di aláìlérè; kò sí ẹni ìtànjẹ.”“Oró paramọ́lẹ̀ ń bẹ lábẹ́ ètè wọn.”
14 “Ẹnu ẹni tí ó kún fún èpè àti fún oró kíkorò.”
15 “Ẹsẹ̀ wọn yára láti ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀:
16 Ìparun àti ìpọ́njú wà lọ́nà wọn.