12 Gbogbo wọn ni ó ti yapa,wọ́n jùmọ̀ di aláìlérè;kò sí ẹni tí ń ṣe rere,kò tilẹ̀ sí ẹnìkan.”
13 “Ibojì tí ó ṣí sílẹ̀ ní Ọ̀fun wọn:ahọ́n wọn di aláìlérè; kò sí ẹni ìtànjẹ.”“Oró paramọ́lẹ̀ ń bẹ lábẹ́ ètè wọn.”
14 “Ẹnu ẹni tí ó kún fún èpè àti fún oró kíkorò.”
15 “Ẹsẹ̀ wọn yára láti ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀:
16 Ìparun àti ìpọ́njú wà lọ́nà wọn.
17 Ọ̀nà àlàáfíà ni wọn kò sì mọ̀:”
18 “Ìbẹ̀rù Ọlọ́run kò sí níwájú wọn.”