Àwọn Ọba Kinni 17:21 BM

21 Elija bá na ara rẹ̀ sórí ọmọ yìí nígbà mẹta, ó sì ké pe OLÚWA, ó ní, “OLUWA Ọlọrun mi, jẹ́ kí ẹ̀mí ọmọ yìí tún pada sinu rẹ̀.”

Ka pipe ipin Àwọn Ọba Kinni 17

Wo Àwọn Ọba Kinni 17:21 ni o tọ