17 “Èyí ni orúkọ àwọn ọkùnrin náà tí yóò pín ilẹ̀, náà fún yín gẹ́gẹ́ bí ogún: Élíásárì àlùfáà àti Jóṣúà ọmọ Núnì.
18 Kí o sì yan olórí kan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan láti pín ilẹ̀ náà.
19 Èyí ni orúkọ wọn:Kálẹ́bù ọmọ Jéfúnè,láti ẹ̀yà Júdà;
20 Ṣémúélì ọmọ Ámíhúdì,láti ẹ̀yà Ṣíméónì;
21 Élídádì ọmọ Kísílónì,láti ẹ̀yà Bẹ́ńjámínì;
22 Búkì ọmọ Jógílì,láti ẹ̀yà olórí àwọn ọmọ Dánì;
23 Háníélì ọmọ Éfódù,láti ẹ̀yà Mánásè, olórí àwọn ọmọ Jóṣẹ́fù,