Nọ́ḿbà 5:21 BMY

21 nígbà náà ni àlùfáà yóò mú obìnrin náà búra, yóò sọ fún obìnrin náà pé: “Kí Olúwa sọ ọ́ di ẹni ègún àti ẹni ìbáwí láàrin àwọn ènìyàn rẹ nípa mímú kí itan rẹ jẹrà, kí ikùn rẹ sì wú.

Ka pipe ipin Nọ́ḿbà 5

Wo Nọ́ḿbà 5:21 ni o tọ