Nọmba 20:18 BM

18 Ṣugbọn àwọn ará Edomu dáhùn pé, “A kò ní jẹ́ kí ẹ gba ilẹ̀ wa kọjá, bí ẹ bá sì fẹ́ kọjá pẹlu agídí, a óo ba yín jagun.”

Ka pipe ipin Nọmba 20

Wo Nọmba 20:18 ni o tọ