19 Àwọn olórí náà nìwọ̀nyí: láti inú ẹ̀yà Juda, a yan Kalebu ọmọ Jefune.
20 Láti inú ẹ̀yà Simeoni, a yan Ṣemueli ọmọ Amihudu.
21 Láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, a yan Elidadi ọmọ Kisiloni.
22 Láti inú ẹ̀yà Dani, a yan Buki ọmọ Jogili.
23 Láti inú ẹ̀yà Manase, a yan Hanieli ọmọ Efodu.
24 Láti inú ẹ̀yà Efuraimu, a yan Kemueli ọmọ Ṣifitani.
25 Láti inú ẹ̀yà Sebuluni, a yan Elisafani ọmọ Parinaki.