26 Nígbà ti Ṣọ́ọ̀lù sì de Jerúsálémù ó pète láti da ara rẹ̀ pọ̀ mọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn; gbogbo wọn sì bẹ̀rù rẹ̀, nítorí wọn kò gbàgbọ́ pé ọmọ-ẹ̀yìn kan ni.
Ka pipe ipin Ìṣe Àwọn Àpósítélì 9
Wo Ìṣe Àwọn Àpósítélì 9:26 ni o tọ