25 Eberi, Pelegi, Reu;
26 Serugi, Nahori, Tẹra;
27 Abramu, tí a tún ń pè ní Abrahamu.
28 Àwọn ọmọ Abrahamu ni Isaaki ati Iṣimaeli.
29 Àkọsílẹ̀ ìran wọn nìyí: Nebaiotu ni àkọ́bí Iṣimaeli, lẹ́yìn náà ni ó bí Kedari, Adibeeli, ati Mibisamu;
30 Miṣima, Duma ati Masa; Hadadi ati Tema;
31 Jeturi, Nafiṣi, ati Kedema.