Kronika Kinni 11:15 BM

15 Ní ọjọ́ kan, mẹta ninu àwọn ọgbọ̀n ọ̀gágun olókìkí lọ sọ́dọ̀ Dafidi nígbà tí ó wà ní ihò Adulamu, nígbà tí àwọn ọmọ ogun Filistini dó sí àfonífojì Refaimu.

Ka pipe ipin Kronika Kinni 11

Wo Kronika Kinni 11:15 ni o tọ