Kronika Kinni 14:11 BM

11 Dafidi bá lọ kọlù wọ́n ní Baali Perasimu, ó sì ṣẹgun wọn, ó ní, “Ọlọrun ti lò mí láti kọlu àwọn ọ̀tá mi bí ìkún omi.” Nítorí náà ni a ṣe ń pe orúkọ ibẹ̀ ní Baali Perasimu.

Ka pipe ipin Kronika Kinni 14

Wo Kronika Kinni 14:11 ni o tọ