11 Nahiṣoni ni baba Salima; Salima ni ó bí Boasi,
12 Boasi bí Obedi, Obedi sì bí Jese.
13 Jese bí ọmọ meje; orúkọ wọn nìyí bí wọ́n ṣe tẹ̀lé ara wọn: Eliabu ni àkọ́bí, lẹ́yìn náà Abinadabu ati Ṣimea;
14 Netaneli ati Radai;
15 Osemu ati Dafidi.
16 Àwọn arabinrin wọn ni Seruaya ati Abigaili. Seruaya yìí ló bí Abiṣai, Joabu ati Asaheli.
17 Abigaili fẹ́ Jeteri láti inú ìran Iṣimaeli, ó sì bí Amasa fún un.