Kronika Kinni 19:10 BM

10 Nígbà tí Joabu rí i pé àwọn ọ̀tá ti gbógun ti òun níwájú ati lẹ́yìn, ó yan àwọn akọni ninu àwọn ọmọ ogun Israẹli láti dojú kọ àwọn ará Siria.

Ka pipe ipin Kronika Kinni 19

Wo Kronika Kinni 19:10 ni o tọ