Kronika Kinni 19:15 BM

15 Nígbà tí àwọn ará Amoni rí i pé àwọn ará Siria sá, àwọn náà sá fun Abiṣai, wọn sì wọ ìlú wọn lọ. Joabu bá pada sí Jerusalẹmu.

Ka pipe ipin Kronika Kinni 19

Wo Kronika Kinni 19:15 ni o tọ