8 Nígbà náà ni Jésè pe Ábínádábù, ó sì jẹ́ kí ó rìn kọjá ní iwájú Sámúẹ́lì. Ṣùgbọ́n Sámúẹ́lì wí pé, “Olúwa kò yan ẹni yìí.”
Ka pipe ipin 1 Sámúẹ́lì 16
Wo 1 Sámúẹ́lì 16:8 ni o tọ