20 “Kí ló dé tí a fi ìmọ́lẹ̀fún ẹni tí ń kérora,tí a fi ẹ̀mí fún ẹni tí inú rẹ̀ bàjẹ́;
21 tí ó ń wá ikú,ṣugbọn tí kò rí;tí ó ń wá ikú lójú mejeejiju ẹni tí ń wá ìṣúra tí a fi pamọ́ lọ?
22 Àwọn tí inú wọn ìbá dùn lọpọlọpọbí wọ́n bá rí ẹni gbé wọn sin.
23 Kí ló dé tí a fi fi ìmọ́lẹ̀fún ẹni tí ọ̀nà dàrú mọ́ lójú;ẹni tí Ọlọrun ti tì sinu àhámọ́?
24 Nítorí ìmí ẹ̀dùn di oúnjẹ fún mi,ìráhùn mi sì ń tú jáde bí omi.
25 Ohun tí mo bẹ̀rù jù ti dé bá mi,ohun tí ń fò mí láyà ti ṣẹlẹ̀ sí mi.
26 N kò ní alaafia,bẹ́ẹ̀ ni ara kò rọ̀ mí,n kò sì ní ìsinmi, àfi ìyọnu.”