34 Àwọn tí wọ́n lóye yóo sọ fún mi,àwọn ọlọ́gbọ́n tí wọn ń gbọ́ mi yóo sọ pẹlu pé,
35 ‘Jobu ń sọ̀rọ̀ láìní ìmọ̀,ó ń sọ̀rọ̀ láìní òye tí ó jinlẹ̀.’
36 À bá lè gbé ọ̀rọ̀ Jobu yẹ̀wò títí dé òpin,nítorí pé ó ń sọ̀rọ̀ bí eniyan burúkú.
37 Ó fi ọ̀tẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá;ó ń pàtẹ́wọ́ ẹlẹ́yà láàrin wa,ó sì ń kẹ́gàn Ọlọrun.”