1 “Ẹ̀mí mi bàjẹ́,ọjọ́ mi ni a tigé kúrú, ìsà òkú dúró dè mí.
2 Nítòótọ́ àwọn ẹlẹ́yà h wà lọ́dọ̀ mi,ojú mi sì tẹ̀mọ́ ìmúnibínú wọn.
3 “Ǹjẹ́ nísinsínyí, fi lélẹ̀ yàn onígbọ̀wọ́fún mi lọ́dọ̀ rẹ; ta ni Olúwa tí yóò le ṣe ààbò fún mi?
4 Nítorí pé ìwọ ti ṣé wọ́n láyà kúrònínú òyè; nítorí náà ìwọ kì yóò gbé wọn lékè.
5 Ẹni tí ó fi àwọn ọ̀rẹ́ hàn fúnìgárá, òun ni ojú àwọn ọmọ rẹ̀ yóò mú òfo.