1 Ígbà náà ní Bílídádì, ará Ṣúà, dáhùn wí pé:
2 “Ìjọba àti ẹ̀ru ḿbẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀,òun ní iṣe ìlàjà ní ibi gígagíga ọ̀run.
3 Àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ ha ní ìyè bí,tàbí ara tani ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ kò tàn sí?
4 Èé ha ti ṣe tí a ó fi dá ènìyàn láre lọ́dọ̀ Ọlọ́run?Tàbí ẹni tí a bí láti inú obìnrin wá yóò ha ṣe mọ́?
5 Kíyèsí i, òṣùpá kò sì lè í tànìmọ́lẹ̀, àní àwọn ìràwọ kò mọ́lẹ̀ ní ojú rẹ̀.
6 Áḿbọ̀torí ènìyàn tí iṣe ìdin, àtiọmọ ènìyàn tí iṣe kòkòrò!”