34 “Àwọn ènìyàn amòye yóò wí fúnmi, àti pẹ̀lúpẹ̀lú ẹnikẹ́ni tí í ṣe ọlọ́gbọ́n tí ó sì gbọ́ mi pé,
35 ‘Jóòbù ti fi àìmọ̀ sọ̀rọ̀, ọ̀rọ̀ rẹ̀ sì ṣealáìgbọ́n.’
36 Ìfẹ́ mi ni kí a dán Jóòbù wò déòpin, nítorí ìdahùn rẹ̀ dà bí i ti ènìyàn búburú:
37 Nítorí pe ó fi ìṣọ̀tẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀; ópàtẹ́wọ́ ní àárin wa, ó sì sọọ̀rọ̀ di púpọ̀ sí Ọlọ́run.”