1 “Ìwọ mọ àkókò ìgbà tíàwọn ewúrẹ́ orí àpáta ìbímọ? Ìwọsì lè kíyèsí ìgbà tí abo àgbọ̀nrín ń bímọ?
2 Ìwọ lè ka iye òṣùpá tí wọn ń pè,ìwọ sì mọ àkókò ìgbà tí wọn ń bímọ,
3 Wọ́n tẹ ara wọn ba, wọ́n bí mọ,wọ́n sì mú ìkáànú wọn jáde.
4 Àwọn ọmọ wọn rí dáradára, wọ́ndàgbà nínú ọ̀dàn; wọ́n jáde lọ, wọn kò sì tún padà wá sọ́dọ̀ wọn.
5 “Ta ni ó jọ̀wọ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ oko lọ́wọ́?Tàbí ta ní ó tú ìdè kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ìgbẹ́,
6 Èyí tí mo fi ihà ṣe ilé fún, àtiilẹ̀ iyọ̀ ní ibùgbé rẹ̀
7 Ó rẹ́rìnín sí ariwo ìlú, bẹ́ẹ̀ niÒun kò sì gbọ́ igbe darandaran.