Jeremáyà 29:22 BMY

22 Nítorí ti wọn, ègún yìí yóò ran gbogbo àwọn àtìpó tó wà ní ilẹ̀ Bábílónì láti Júdà: ‘Ọlọ́run yóò ṣe yín bí i Sedekáyà àti Áhábù tí Ọba Bábílónì dáná sun.’

Ka pipe ipin Jeremáyà 29

Wo Jeremáyà 29:22 ni o tọ