15 Nítorí á jí mi gbé tà kúrò ní ilẹ̀ àwọn Ébérù ni, àti pé níhìnín èmi kò ṣe ohunkóhun tí ó fi yẹ kí èmi wà ní ìhámọ́ bí mo ti wà yìí.”
Ka pipe ipin Jẹ́nẹ́sísì 40
Wo Jẹ́nẹ́sísì 40:15 ni o tọ