3 Wò mí kí o sì dá mi lóhùn, Olúwa Ọlọ́run mi.Fi ìmọ́lẹ̀ fún ojú mi, kí èmi ó má sùn oorun ikú;
4 Ọ̀tá mi wí pé, “Èmi ti ṣẹ́gun Rẹ̀,”àwọn ọ̀ta mi yóò yọ̀ tí mo bá ṣubú.
5 Ṣùgbọ́n mo gbẹ́kẹ̀lé ìfẹ́ Rẹ tí kì í kùnà;ọkàn mi ń yọ̀ nínú ìgbàlà Rẹ.
6 Èmi ó kọrin sí Olúwa,nítorí ó dára sí mi.