9 Ìwọ yóò fi ọ̀pá irin ṣe àkóso wọnìwọ yóò sì rún wọn wómú wómú bí ìkòkò amọ̀”.
10 Nítorí náà, ẹ̀yin ọba, ẹ jẹ́ ọlọgbọ́n;ẹ gbọ́ ìkìlọ̀ ẹ̀yin alákòóso ayé.
11 Ẹ ṣin Olúwa pẹ̀lú ìbẹ̀rùẹ sì máa yọ̀ pẹ̀lú ìwárìrì.
12 Fi ẹnu ko ọmọ náà ní ẹnu, kí ó má ba à bínúkí ó má ba à payin run ní ọ̀nà yin,nítorí ìbínú Rẹ̀ lè ru sókè ní ẹ̀ẹ̀kan.Ìbùkún ni fún gbogbo àwọn tí ó fi i ṣe ibi ìsádi wọn.