6 Àwọn orílẹ̀ èdè ń bínú, àwọn ilẹ̀ ọba subúó gbé ohun Rẹ̀ sókè, ayé yọ̀.
7 Ọlọ́run awọn ọmọ ogún wà pẹ̀lú waỌlọ́run Jákọ́bù ni ààbò wa
8 Ẹ wá wo iṣẹ́ Olúwairú ahoro tí ó ṣe ní ayé
9 O mú ọ̀tẹ̀ tán de òpin ilẹ̀ ayéó ṣẹ́ ọrun, ó sì gé ọ̀kọ̀ sí méjìó fi kẹ̀kẹ́ ogun jóná
10 Ẹ dúró jẹ́ẹ kí ẹ sì mọ̀ pé èmi ní Ọlọ́runA ó gbé mi ga nínú àwọn orílẹ̀ èdèA o gbé mi ga ní ayé.
11 Ọlọ́run alágbára wà pẹ̀lú waỌlọ́run Jákọ́bù sì ni ààbò wa.