7 Nítorí òun ni Ọlọ́run waàwa sì ni ènìyàn pápá Rẹ̀,àti ọ̀wọ́ ẹran ni abẹ́ ìpamọ́ Rẹ̀Lónìí ti ìwọ bá gbọ́ ohùn Rẹ̀,
8 Ẹ má ṣe sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ní Méríbà,àti bí ẹ ti ṣe ní ọjọ́ náà ni Másà ni ihà,
9 Nígbà ti àwọn baba yin dán mi wòti wọn wádìí mi,ti wọn sì ri iṣẹ́ mi
10 Fún ogójì ọdún ni èmi fi bínú sí ìran náà;mo wí pé, “Wọ́n jẹ́ ènìyàn tí ọkàn wọn sáko lọwọn kò sì mọ ọ̀nà mi”.
11 Nítorí náà ni mo kéde ìbúra nínú ìbínú mi“Wọn kì yóò wọ ibi ìsinmi mi.”